1 Ní ẹ̀bá odò Babeli, níbẹ̀ ni àwa gbé jókòó
2 Àwa fi dùùrù wa kọ́ sí orí igi wílò,
3 Nítorí pé níbẹ̀ ni àwọn
4 Àwa ó ti ṣe kọ orin
5 Jerusalẹmu, bí èmi bá gbàgbé rẹ
6 Bí èmi kò bá rántí rẹ,
7 Olúwa rántí ọjọ́ Jerusalẹmu,
8 Ìwọ, ọmọbìnrin Babeli, ẹni tí a ó parun;
9 Ìbùkún ni fún ẹni tí ó mú ọmọ wẹ́wẹ́ rẹ