1 Ìbùkún ni fún gbogbo ẹni tí ó bẹ̀rù Olúwa:
2 Nítorí tí ìwọ yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ
3 Obìnrin rẹ yóò dàbí àjàrà rere
4 Kíyèsi i pé, bẹ́ẹ̀ ni a ó bùsi i fún ọkùnrin náà,
5 Kí Olúwa kí ó bùsi i fún ọ láti Sioni wá,
6 Bẹ́ẹ̀ ni kí ìwọ kí ó sì máa rí àti ọmọdọ́mọ rẹ.