Salmos 127

YOR

1 Bí kò ṣe pé Olúwa bá kọ́ ilé náà

2 Asán ni fún ẹ̀yin ti ẹ dìde ní kùtùkùtù

3 Kíyèsi i, àwọn ọmọ ni ìní Olúwa:

4 Bí ọfà ti rí ní ọwọ́ alágbára,

5 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí apó rẹ̀ kún fún wọn;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado