Salmos 126

YOR

1 Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà,

2 Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín,

3 Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa;

4 Olúwa mú ìkólọ wa padà,

5 Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn

6 Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado