Salmos 107

YOR

1 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó ṣeun;

2 Jẹ́ kí àwọn ẹni ìràpadà Olúwa kí ó wí báyìí,

3 àwọn tí ó kójọ láti ilẹ̀ wọ̀n-ọn-nì,

4 Wọ́n ń rìn káàkiri ní aginjù ní ibi tí ọ̀nà kò sí,

5 Ebi ń pa wọn, òǹgbẹ gbẹ wọ́n,

6 Ní ìgbà náà, wọ́n kígbe sókè

7 Ó fi ọ̀nà títọ́ hàn wọ́n sí ìlú

8 Ẹ jẹ́ kí wọn máa yin Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́

9 nítorí tí ó tẹ́ ìfẹ́ ọkàn lọ́run

10 Ọ̀pọ̀ jókòó nínú òkùnkùn àti òjìji ikú,

11 nítorí tí wọ́n ṣe àìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀

12 Ó sì fi ìkorò rẹ àyà wọn sílẹ̀;

13 Ní ìgbà náà wọ́n ké pe

14 Ó mú wọn jáde kúrò nínú

15 Ẹ jẹ́ kí wọn fi ọpẹ́ fún Olúwa! Nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ sí ọmọ ènìyàn.

16 Nítorí tí ó já ìlẹ̀kùn idẹ wọ̀n-ọn-nì

17 Ọ̀pọ̀ di aṣiwèrè nítorí ìrékọjá wọn

18 Wọ́n kọ gbogbo oúnjẹ

19 Nígbà náà wọ́n kígbe sí Olúwa nínú ìṣòro wọn,

20 Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀, ara wọn sì dá

21 Ẹ jẹ́ kí wọ́n fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ fún ọmọ ènìyàn.

22 Jẹ́ kí wọn rú ẹbọ ọpẹ́

23 Àwọn tí ń sọ̀kalẹ̀ lọ sí Òkun nínú ọkọ̀ ojú omi,

24 Wọ́n rí iṣẹ́ Olúwa,

25 Nítorí tí ó pàṣẹ, ó sì mú ìjì fẹ́

26 Wọ́n gòkè lọ sí ọ̀run wọ́n sì

27 Wọ́n ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n bí ọ̀mùtí ènìyàn:

28 Nígbà náà wọ́n ń kígbe sókè

29 Ó sọ ìjì di ìdákẹ́rọ́rọ́

30 Inú wọn dùn nígbà tí ara wọn balẹ̀,

31 Jẹ́ kí wọn fi ọpẹ́ fún

32 Jẹ́ kí wọn gbé e ga ní àárín àwọn ènìyàn

33 Ó sọ odò di aginjù,

34 Ilẹ̀ eléso di aṣálẹ̀

35 O sọ aginjù di adágún omi àti

36 níbẹ̀ ó mú ẹni tí ebi ń pa wà,

37 Wọn fún irúgbìn, wọ́n sì gbin ọgbà àjàrà

38 Ó bùkún wọn, wọ́n sì pọ̀ sí i ní iye

39 Nígbà náà, ọjọ́ wọn kúrú,

40 ẹni tí ó da ẹ̀gàn lu ọmọ-aládé

41 Ṣùgbọ́n ó gbé aláìní sókè kúrò nínú ìnira

42 Àwọn tí ó dúró sì rí i, inú wọn sì dùn

43 Ẹni tí ó bá gbọ́n, jẹ́ kí ó kíyèsi nǹkan wọ̀nyí

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado