1 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó ṣeun;
2 Jẹ́ kí àwọn ẹni ìràpadà Olúwa kí ó wí báyìí,
3 àwọn tí ó kójọ láti ilẹ̀ wọ̀n-ọn-nì,
4 Wọ́n ń rìn káàkiri ní aginjù ní ibi tí ọ̀nà kò sí,
5 Ebi ń pa wọn, òǹgbẹ gbẹ wọ́n,
6 Ní ìgbà náà, wọ́n kígbe sókè
7 Ó fi ọ̀nà títọ́ hàn wọ́n sí ìlú
8 Ẹ jẹ́ kí wọn máa yin Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́
9 nítorí tí ó tẹ́ ìfẹ́ ọkàn lọ́run
10 Ọ̀pọ̀ jókòó nínú òkùnkùn àti òjìji ikú,
11 nítorí tí wọ́n ṣe àìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀
12 Ó sì fi ìkorò rẹ àyà wọn sílẹ̀;
13 Ní ìgbà náà wọ́n ké pe
14 Ó mú wọn jáde kúrò nínú
15 Ẹ jẹ́ kí wọn fi ọpẹ́ fún Olúwa! Nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti nítorí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ sí ọmọ ènìyàn.
16 Nítorí tí ó já ìlẹ̀kùn idẹ wọ̀n-ọn-nì
17 Ọ̀pọ̀ di aṣiwèrè nítorí ìrékọjá wọn
18 Wọ́n kọ gbogbo oúnjẹ
19 Nígbà náà wọ́n kígbe sí Olúwa nínú ìṣòro wọn,
20 Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀, ara wọn sì dá
21 Ẹ jẹ́ kí wọ́n fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí ìṣeun ìfẹ́ rẹ̀ àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ fún ọmọ ènìyàn.
22 Jẹ́ kí wọn rú ẹbọ ọpẹ́
23 Àwọn tí ń sọ̀kalẹ̀ lọ sí Òkun nínú ọkọ̀ ojú omi,
24 Wọ́n rí iṣẹ́ Olúwa,
25 Nítorí tí ó pàṣẹ, ó sì mú ìjì fẹ́
26 Wọ́n gòkè lọ sí ọ̀run wọ́n sì
27 Wọ́n ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n bí ọ̀mùtí ènìyàn:
28 Nígbà náà wọ́n ń kígbe sókè
29 Ó sọ ìjì di ìdákẹ́rọ́rọ́
30 Inú wọn dùn nígbà tí ara wọn balẹ̀,
31 Jẹ́ kí wọn fi ọpẹ́ fún
32 Jẹ́ kí wọn gbé e ga ní àárín àwọn ènìyàn
33 Ó sọ odò di aginjù,
34 Ilẹ̀ eléso di aṣálẹ̀
35 O sọ aginjù di adágún omi àti
36 níbẹ̀ ó mú ẹni tí ebi ń pa wà,
37 Wọn fún irúgbìn, wọ́n sì gbin ọgbà àjàrà
38 Ó bùkún wọn, wọ́n sì pọ̀ sí i ní iye
39 Nígbà náà, ọjọ́ wọn kúrú,
40 ẹni tí ó da ẹ̀gàn lu ọmọ-aládé
41 Ṣùgbọ́n ó gbé aláìní sókè kúrò nínú ìnira
42 Àwọn tí ó dúró sì rí i, inú wọn sì dùn
43 Ẹni tí ó bá gbọ́n, jẹ́ kí ó kíyèsi nǹkan wọ̀nyí