Salmos 105

YOR

1 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ké pe orúkọ rẹ̀,

2 Kọrin sí i, kọrin ìyìn sí i;

3 Ṣògo nínú orúkọ mímọ́ rẹ̀,

4 Wá Olúwa àti ipá rẹ̀;

5 Rántí àwọn ìyanu tí ó ti ṣe,

6 ẹ̀yin ìran Abrahamu ìránṣẹ́ rẹ̀,

7 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa:

8 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,

9 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,

10 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu gẹ́gẹ́ bí àṣẹ,

11 “Fún ìwọ ni èmi ó fún ní ilẹ̀ Kenaani

12 Nígbà tí wọn kéré níye,

13 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè,

14 Kò gba ẹnikẹ́ni láààyè láti pọ́n wọn lójú;

15 “Má ṣe fọwọ́ kan ẹni àmì òróró mi; má sì ṣe wòlíì mi níbi.”

16 Ó pe ìyàn sórí ilẹ̀ náà

17 Ó sì rán ọkùnrin kan síwájú wọn

18 Wọn fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ bọ ẹsẹ̀ rẹ̀

19 títí ọ̀rọ̀ tí ó sọtẹ́lẹ̀ fi ṣẹ

20 Ọba ránṣẹ́ lọ tú u sílẹ̀

21 Ó fi jẹ olúwa lórí ilẹ̀ rẹ̀,

22 gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, kí ó máa

23 Israẹli wá sí Ejibiti;

24 Olúwa, sì mú àwọn ọmọ rẹ̀ bí sí i

25 Ó yí wọn lọ́kàn padà láti kórìíra àwọn ènìyàn

26 Ó rán Mose ìránṣẹ́ rẹ̀,

27 Wọ́n ń ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrín wọn

28 Ó rán òkùnkùn, o sì mú ilẹ̀ ṣú

29 Ó sọ omi wọn di ẹ̀jẹ̀,

30 Ilẹ̀ mú ọ̀pọ̀lọ́ jáde wá,

31 Ó sọ̀rọ̀, onírúurú eṣinṣin sì dìde,

32 Ó sọ òjò di yìnyín,

33 Ó lu àjàrà wọn àti igi ọ̀pọ̀tọ́ wọn

34 Ó sọ̀rọ̀, eṣú sì dé,

35 wọn sì jẹ gbogbo ewé ilẹ̀ wọn,

36 Nígbà náà, ó kọlu gbogbo àwọn ilẹ̀ wọn,

37 Ó mú Israẹli jáde

38 Inú Ejibiti dùn nígbà tí wọn ń lọ,

39 Ó ta àwọsánmọ̀ fún ìbòrí,

40 Wọn béèrè, ó sì mú ẹyẹ àparò wá,

41 Ó sì la àpáta, ó sì mú omi jáde;

42 Nítorí ó rántí ìlérí mímọ́ rẹ̀

43 Ó sì fi ayọ̀ mú àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde

44 Ó fún wọn ní ilẹ̀ ìní náà,

45 kí wọn kí ó lè máa pa àṣẹ rẹ̀ mọ́

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado