1 Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi; àti gbogbo ohun tí ó wà nínú mi, yín orúkọ rẹ̀ mímọ́.
2 Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi, kí o má ṣe gbàgbé gbogbo oore rẹ̀,
3 ẹni tí ó dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jì ọ́
4 ẹni tí ó ra ẹ̀mí rẹ padà kúrò nínú kòtò ikú
5 ẹni tí ó fi ohun dídára tẹ́ ọ lọ́rùn
6 Olúwa ń ṣe òdodo àti ìdájọ́ fún
7 Ó fi ọ̀nà rẹ̀ hàn fún Mose, iṣẹ́ rẹ̀ fun àwọn ọmọ Israẹli;
8 Olúwa ni aláàánú àti olóore,
9 Òun kì í bá ni wí ní ìgbà gbogbo
10 Òun kì í ṣe sí wa gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ wa
11 Nítorí bí ọ̀run ṣe ga sílẹ̀,
12 Bí ìlà-oòrùn ti jìnnà sí ìwọ̀-oòrùn
13 Bí baba ti ń ṣe ìyọ́nú sí àwọn ọmọ rẹ̀,
14 nítorí tí ó mọ dídá wa,
15 Bí ó ṣe ti ènìyàn ni, ọjọ́ rẹ̀ dàbí koríko,
16 afẹ́fẹ́ fẹ́ kọjá lọ lórí rẹ̀,
17 Ṣùgbọ́n láti ayérayé ni ìfẹ́
18 sí àwọn tí ó pa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́
19 Olúwa ti pèsè ìtẹ́ rẹ̀ nínú ọ̀run,
20 Yin Olúwa, ẹ̀yin angẹli rẹ̀,
21 Yin Olúwa, ẹ̀yin ogun ọ̀run rẹ̀ gbogbo,
22 Yin Olúwa, gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ ní