1 Ọgbọ́n ti kọ́ ilé rẹ̀,
2 ó ti fi ilé pọn tí, ó ti fọ̀nà rokà.
3 ó ti rán àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ jáde, ó sì ń pè,
4 “Jẹ́ kí gbogbo àwọn aláìgbọ́n wọ ibí wá!”
5 “Wá, ẹ wá jẹ́ oúnjẹ mi
6 Fi ìwà àìmọ̀kan rẹ sílẹ̀ ìwọ yóò sì yè;
7 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá bá ẹlẹ́gàn wí, kọ lẹ́tà sí àbùkù
8 Má ṣe bá ẹlẹ́gàn wí, àìṣe bẹ́ẹ̀ yóò kórìíra rẹ.
9 kọ́ ọlọ́gbọ́n ènìyàn lẹ́kọ̀ọ́, yóò sì gbọ́n sí i
10 “Ìbẹ̀rù Olúwa ni ìbẹ̀rẹ̀ ọgbọ́n,
11 Nítorí nípasẹ̀ mi ọjọ́ rẹ yóò gùn
12 Bí ìwọ bá gbọ́n, ọgbọ́n rẹ yóò fún ọ ní èrè:
13 Òmùgọ̀ obìnrin jẹ́ aláriwo;
14 Ó jókòó ní ẹnu-ọ̀nà ilé rẹ̀
15 ó ń pe àwọn tí ó ń kọjá lọ,
16 “Jẹ́ kí gbogbo ẹni tí ó jẹ́ aláìlóye súnmọ́ bí!”
17 “Omi tí a jí mu dùn
18 Ṣùgbọ́n wọn ò funra pé àwọn òkú wà níbẹ̀,