Provérbios 7

YOR

1 Ọmọ mi, pa ọ̀rọ̀ mi mọ́,

2 Pa òfin mi mọ́, ìwọ yóò sì yè

3 Kọ wọ́n sí ọwọ́ òsì rẹ, má ṣe fi jẹun

4 Wí fún ọgbọ́n pé, “Ìwọ ni arábìnrin mi,”

5 Wọn yóò pa ó mọ́ kúrò lọ́wọ́ obìnrin alágbèrè,

6 Ní ojú fèrèsé ilé è mi

7 Mo rí i láàrín àwọn aláìmọ̀kan

8 Ó ń lọ ní pópónà ní tòsí i ilé alágbèrè obìnrin náà,

9 Ní ìrọ̀lẹ́ bí oòrùn ṣe ń wọ̀,

10 Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin kan jáde wá láti pàdé rẹ̀,

11 (Ó jẹ́ aláriwo àti alágídí,

12 bí ó ti ń já níhìn-ín ní ó ń já lọ́hùn ún

13 Ó dìímú, ó sì fẹnukò ó ní ẹnu

14 “Mo ní ọrẹ àlàáfíà ní ilé;

15 Nítorí náà ni n o ṣe jáde wá pàdé è rẹ;

16 Mo ti tẹ́ ibùsùn mi

17 Mo ti fi nǹkan olóòórùn dídùn sí ibùsùn mi

18 Wá, jẹ́ kí a lo ìfẹ́ papọ̀ ní kíkún títí di àárọ̀;

19 Ọkọ ọ̀ mi ò sí nílé;

20 Ó mú owó púpọ̀ lọ́wọ́

21 Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ dídùn ó sì í lọ́nà;

22 Òun sì tọ̀ ọ́ lọ lẹsẹ̀ kan náà,

23 Títí tí ọ̀kọ̀ fi gún un ní ẹ̀dọ̀,

24 Nítorí náà báyìí ẹ̀yin ọmọ mi, tẹ́tí sí mi

25 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn rẹ kí ó yà sí ọ̀nà rẹ̀,

26 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn tí ó ti fà lulẹ̀.

27 Ilé e rẹ̀ ni ọ̀nà tààrà sí isà òkú,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado