Provérbios 6

YOR

1 Ọmọ mi, bí ìwọ bá ṣe onídùúró fún aládùúgbò rẹ,

2 bí a bá ti fi ọ̀rọ̀ tí ó sọ dẹkùn mú ọ,

3 Nígbà náà, ṣe èyí, ìwọ ọmọ mi, láti gba ara rẹ

4 Má ṣe jẹ́ kí oorun kí ó kùn ọ́,

5 Gba ara rẹ sílẹ̀, bí abo èsúró kúrò lọ́wọ́ ọdẹ,

6 Tọ èèrà lọ, ìwọ ọ̀lẹ;

7 Kò ní olùdarí,

8 síbẹ̀, a kó ìpèsè rẹ̀ jọ ní àsìkò òjò

9 Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò dùbúlẹ̀, ìwọ ọ̀lẹ?

10 Oorun díẹ̀, òògbé díẹ̀,

11 Òsì yóò sì wá sórí rẹ bí ìgárá ọlọ́ṣà

12 Ènìyànkénìyàn àti ènìyàn búburú,

13 tí ó ń ṣẹ́jú pàkòpàkò,

14 tí ó ń pète búburú pẹ̀lú ẹ̀tàn nínú ọkàn rẹ̀

15 Nítorí náà ìdààmú yóò dé bá a ní ìṣẹ́jú akàn;

16 Àwọn ohun mẹ́fà wà tí Olúwa kórìíra,

17 Ojú ìgbéraga,

18 ọkàn tí ń pète ohun búburú,

19 ajẹ́rìí èké tí ń tú irọ́ jáde lẹ́nu

20 Ọmọ mi, pa àṣẹ baba rẹ mọ́

21 Jẹ́ kí wọn wà nínú ọkàn rẹ láéláé

22 Nígbà tí ìwọ bá ń rìn, wọn yóò ṣe amọ̀nà rẹ;

23 Nítorí àwọn àṣẹ yìí jẹ́ fìtílà,

24 Yóò pa ọ́ mọ́ kúrò lọ́wọ́ obìnrin búburú,

25 Má ṣe ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ si nínú ọkàn rẹ nítorí ẹwà rẹ

26 Nítorí pé nípasẹ̀ àgbèrè obìnrin ni ènìyàn fi ń di oníṣù-àkàrà kan,

27 Ǹjẹ́ ọkùnrin ha le è gbé iná lé orí itan

28 Ǹjẹ́ ènìyàn le è máa rìn lórí iná?

29 Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń lọ sùn pẹ̀lú aya aláya;

30 Àwọn ènìyàn kì í kẹ́gàn olè tí ó bá jalè

31 Síbẹ̀ bí ọwọ́ bá tẹ̀ ẹ́, ó gbọdọ̀ san ìlọ́po méje

32 Ṣùgbọ́n ẹni tí ń ṣe àgbèrè kò nírònú;

33 Ìfarapa àti ìtìjú ni tirẹ̀,

34 Nítorí owú yóò ru ìbínú ọkọ sókè,

35 Kò nígbà nǹkan kan bí ohun ìtánràn;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado