Provérbios 4

YOR

1 Tẹ́tí, ẹ̀yin ọmọ mi, sí ẹ̀kọ́ baba; fetísílẹ̀ kí o sì ní òye sí i.

2 Mo fún ọ ní ẹ̀kọ́ tí ó yè kooro,

3 Nígbà tí mo jẹ́ ọ̀dọ́mọkùnrin ní ilé baba à mí,

4 Ó kọ́ mi ó sì wí pé,

5 Gba ọgbọ́n, gba òye,

6 Má ṣe kọ ọgbọ́n sílẹ̀, yóò sì dáàbò bò ọ́,

7 Ọgbọ́n ni ó ga jù; nítorí náà gba ọgbọ́n.

8 Gbé e ga, yóò sì gbé ọ ga

9 Yóò fi òdòdó ọ̀ṣọ́ ẹwà sí orí rẹ

10 Tẹ́tí, ọmọ mi, gba ohun tí mo sọ,

11 Mo tọ́ ọ ṣọ́nà ní ọ̀nà ti ọgbọ́n

12 Nígbà tí o rìn, ìgbésẹ̀ rẹ kò ní ní ìdíwọ́

13 Di ẹ̀kọ́ mú, má ṣe jẹ́ kí ó lọ;

14 Má ṣe gbé ẹsẹ̀ rẹ sí ojú ọnà àwọn ènìyàn búburú

15 Yẹra fún un, má ṣe rìn níbẹ̀;

16 Nítorí wọn kò le sùn àyàfi tí wọ́n bá ṣe ibi,

17 Wọ́n ń jẹ oúnjẹ ìwà búburú

18 Ipa ọ̀nà olódodo dàbí àṣẹ̀ṣẹ̀yọ oòrùn

19 ṣùgbọ́n ọ̀nà ènìyàn búburú dàbí òkùnkùn biribiri;

20 Ọmọ mi, tẹ́tí sí ohun tí mo sọ;

21 Má ṣe jẹ́ kí wọ́n rá mọ́ ọ lójú

22 nítorí ìyè ni wọ́n jẹ́ fún gbogbo ẹni tí ó rí wọn

23 Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́,

24 Mú àrékérekè kúrò ní ẹnu rẹ;

25 Jẹ́ kí ojú rẹ máa wo iwájú,

26 Kíyèsi ìrìn ẹsẹ̀ rẹ

27 Má ṣe yà sọ́tùn ún tàbí sósì;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado