Provérbios 29

YOR

1 Ẹni tí ó sì ń ṣorí kunkun lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbáwí

2 Nígbà tí olódodo bá ń gbilẹ̀, àwọn ènìyàn a yọ̀

3 Ènìyàn tí ó fẹ́ràn ọgbọ́n mú kí baba rẹ̀ láyọ̀

4 Nípa ìdájọ́ òdodo ni ọba fi í mú ìlú tòrò nini,

5 Ẹnikẹ́ni tí ó bá tan aládùúgbò rẹ̀

6 Ẹ̀ṣẹ̀ ènìyàn ibi ni ó jẹ́ ìdẹ̀kùn rẹ̀

7 Olódodo ń máa ro ọ̀rọ̀ tálákà,

8 Àwọn ẹlẹ́yà a máa ru ìlú sókè,

9 Bí ọlọ́gbọ́n ènìyàn bá lọ sí ilé ẹjọ́ pẹ̀lú aláìgbọ́n

10 Àwọn tí ó ń tàjẹ̀ sílẹ̀ kò rí ẹni dídúró ṣinṣin

11 Aláìgbọ́n ènìyàn fi gbogbo ẹnu rẹ̀ bínú

12 Bí olórí bá fetí sí irọ́,

13 Tálákà ènìyàn àti aninilára jọ ní àbùdá yìí,

14 Bí ọba kan bá ń ṣe ìdájọ́ tálákà pẹ̀lú òtítọ́

15 Ọ̀pá ìbániwí ń fún ni ní ọgbọ́n

16 Nígbà tí ènìyàn búburú ń gbilẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà ni ẹ̀ṣẹ̀ ń gbilẹ̀

17 Bá ọmọ rẹ wí, yóò sì fún ọ ní àlàáfíà

18 Níbi tí kò ti sí ìfihàn, àwọn ènìyàn a gbé ìgbé ayé àìbìkítà,

19 A kò le fi ọ̀rọ̀ lásán kìlọ̀ fún ìránṣẹ́

20 Ǹjẹ́ ó rí ènìyàn tí ń kánjú sọ̀rọ̀?

21 Bí ènìyàn kan bá kẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ lákẹ̀ẹ́jù láti kékeré

22 Oníbìínú ènìyàn a ru ìjà sókè,

23 Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ọ́ di ẹni ilẹ̀

24 Ẹni tí ó ń kó ẹgbẹ́, olè kórìíra ọkàn ara rẹ̀,

25 Ìbẹ̀rù ènìyàn kan yóò sì di ìdẹ̀kùn

26 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ń wá ojúrere alákòóso,

27 Olódodo kórìíra àwọn aláìṣòótọ́:

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado