Provérbios 28

YOR

1 Ènìyàn búburú ń sá bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹnìkan kò lé e

2 Nígbà tí orílẹ̀-èdè bá ní orí kunkun, àwọn ọba rẹ̀ a máa pọ̀,

3 Ọba tí ó ni àwọn tálákà lára

4 Àwọn tí ó kọ òfin sílẹ̀ a máa gbóríyìn fún ènìyàn búburú

5 Òye ìdájọ́ òdodo kò yé àwọn ẹni ibi

6 Ó sàn láti jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ jẹ́ aláìlábùkù

7 Ẹni tí ó pa òfin mọ́ jẹ́ olóye ọmọ

8 Ẹni tí ó mú ọrọ̀ rẹ̀ di púpọ̀ nípa èrè àjẹjù

9 Bí ẹnikẹ́ni bá kọ etí ikún sí òfin,

10 Ẹni tí ó mú olódodo rìn ọ̀nà búburú

11 Ọlọ́rọ̀ ènìyàn le è gbọ́n lójú ara rẹ̀

12 Nígbà tí olódodo ń lékè ariwo ayọ̀ ta;

13 Ẹni tí ó bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ kì yóò ṣe rere,

14 Ìbùkún ni fún ènìyàn náà tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run nígbà gbogbo

15 Bí kìnnìún tí ń ké tàbí Beari tí ń halẹ̀

16 Ọmọ-aládé tí ó ṣe aláìmòye púpọ̀ ní ń ṣe ìwà ìkà púpọ̀ pẹ̀lú,

17 Ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò balẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn

18 Ẹni tí ń rìn déédéé ní yóò là,

19 Ẹni tí ó bá ro ilẹ̀ rẹ̀ yóò ní oúnjẹ lọ́pọ̀lọ́pọ̀

20 Olóòtítọ́ ènìyàn yóò rí ìbùkún gbà gan an

21 Ojúsàájú ṣíṣe kò dára,

22 Ahun ń sáré àti là

23 Ẹni tí ó bá ènìyàn kan wí yóò rí ojúrere ni nígbẹ̀yìn

24 Ẹni tí ó ja baba tàbí ìyá rẹ̀ lólè

25 Ọ̀kánjúwà ènìyàn a máa dá ìjà sílẹ̀,

26 Ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀lé ara rẹ̀ jẹ́ aláìgbọ́n

27 Ẹni tí ó ń fi fún tálákà kì yóò ṣe aláìní ohunkóhun,

28 Nígbà tí ènìyàn búburú bá dórí ìjọba, àwọn ènìyàn a na pápá bora;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado