1 Ènìyàn búburú ń sá bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹnìkan kò lé e
2 Nígbà tí orílẹ̀-èdè bá ní orí kunkun, àwọn ọba rẹ̀ a máa pọ̀,
3 Ọba tí ó ni àwọn tálákà lára
4 Àwọn tí ó kọ òfin sílẹ̀ a máa gbóríyìn fún ènìyàn búburú
5 Òye ìdájọ́ òdodo kò yé àwọn ẹni ibi
6 Ó sàn láti jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ jẹ́ aláìlábùkù
7 Ẹni tí ó pa òfin mọ́ jẹ́ olóye ọmọ
8 Ẹni tí ó mú ọrọ̀ rẹ̀ di púpọ̀ nípa èrè àjẹjù
9 Bí ẹnikẹ́ni bá kọ etí ikún sí òfin,
10 Ẹni tí ó mú olódodo rìn ọ̀nà búburú
11 Ọlọ́rọ̀ ènìyàn le è gbọ́n lójú ara rẹ̀
12 Nígbà tí olódodo ń lékè ariwo ayọ̀ ta;
13 Ẹni tí ó bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ kì yóò ṣe rere,
14 Ìbùkún ni fún ènìyàn náà tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run nígbà gbogbo
15 Bí kìnnìún tí ń ké tàbí Beari tí ń halẹ̀
16 Ọmọ-aládé tí ó ṣe aláìmòye púpọ̀ ní ń ṣe ìwà ìkà púpọ̀ pẹ̀lú,
17 Ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò balẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn
18 Ẹni tí ń rìn déédéé ní yóò là,
19 Ẹni tí ó bá ro ilẹ̀ rẹ̀ yóò ní oúnjẹ lọ́pọ̀lọ́pọ̀
20 Olóòtítọ́ ènìyàn yóò rí ìbùkún gbà gan an
21 Ojúsàájú ṣíṣe kò dára,
22 Ahun ń sáré àti là
23 Ẹni tí ó bá ènìyàn kan wí yóò rí ojúrere ni nígbẹ̀yìn
24 Ẹni tí ó ja baba tàbí ìyá rẹ̀ lólè
25 Ọ̀kánjúwà ènìyàn a máa dá ìjà sílẹ̀,
26 Ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀lé ara rẹ̀ jẹ́ aláìgbọ́n
27 Ẹni tí ó ń fi fún tálákà kì yóò ṣe aláìní ohunkóhun,
28 Nígbà tí ènìyàn búburú bá dórí ìjọba, àwọn ènìyàn a na pápá bora;