Provérbios 27

YOR

1 Má ṣe yangàn nítorí ọ̀la

2 Jẹ́ kí ẹlòmíràn yìn ọ́ dípò ẹnu ara rẹ,

3 Òkúta wúwo, erùpẹ̀ sì wúwo

4 Ìbínú ni ìkà, ìrunú sì burú púpọ̀

5 Ìbániwí gbangba sàn

6 Òtítọ́ ni ọgbẹ́ ọ̀rẹ́,

7 Kódà oyin kò dùn lẹ́nu ẹni tí ó ti yó

8 Bí ẹyẹ tí ó ṣáko lọ kúrò níbi ìtẹ́ rẹ̀

9 Ìpara olóòórùn dídùn àti tùràrí ń mú ayọ̀ wá sínú ọkàn

10 Má ṣe kọ ọ̀rẹ́ rẹ àti ọ̀rẹ́ baba rẹ sílẹ̀,

11 Gbọ́n, ọmọ mi, kí o sì mú ayọ̀ wá sínú ọkàn mi

12 Ọlọ́gbọ́n rí ewu, ó sì fi ara pamọ́

13 Gba aṣọ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àjèjì

14 Bí ènìyàn kan ń kígbe súre fún aládùúgbò rẹ ní òwúrọ̀

15 Àyà tí ó máa ń jà dàbí

16 dídá a lẹ́kun dàbí ìgbà tí ènìyàn ń dá afẹ́fẹ́ lẹ́kun

17 Bí irin tí ń pọ́n irin mú

18 Ẹni tí ó tọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́ yóò jẹ èso rẹ̀

19 Bí omi tí ń ṣe àfihàn ojú, nígbà tí a bá wò ó

20 Kò tẹ́ ikú àti ìparun lọ́rùn rí

21 Iná fún fàdákà iná ìléru fún wúrà,

22 Bí a tilẹ̀ gún aláìgbọ́n nínú odó,

23 Rí i dájú pé o mọ ipò tí àwọn agbo àgùntàn rẹ wà

24 nítorí ọrọ̀ kì í pẹ́ lọ títí

25 Nígbà tí a bá kó koríko, ewéko tuntun yóò sì hù jáde, a ó sì kó koríko àwọn orí òkè wọlé

26 àwọn àgùntàn yóò pèsè aṣọ fún ọ,

27 Ìwọ yóò ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàrà ewúrẹ́

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado