1 Má ṣe yangàn nítorí ọ̀la
2 Jẹ́ kí ẹlòmíràn yìn ọ́ dípò ẹnu ara rẹ,
3 Òkúta wúwo, erùpẹ̀ sì wúwo
4 Ìbínú ni ìkà, ìrunú sì burú púpọ̀
5 Ìbániwí gbangba sàn
6 Òtítọ́ ni ọgbẹ́ ọ̀rẹ́,
7 Kódà oyin kò dùn lẹ́nu ẹni tí ó ti yó
8 Bí ẹyẹ tí ó ṣáko lọ kúrò níbi ìtẹ́ rẹ̀
9 Ìpara olóòórùn dídùn àti tùràrí ń mú ayọ̀ wá sínú ọkàn
10 Má ṣe kọ ọ̀rẹ́ rẹ àti ọ̀rẹ́ baba rẹ sílẹ̀,
11 Gbọ́n, ọmọ mi, kí o sì mú ayọ̀ wá sínú ọkàn mi
12 Ọlọ́gbọ́n rí ewu, ó sì fi ara pamọ́
13 Gba aṣọ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àjèjì
14 Bí ènìyàn kan ń kígbe súre fún aládùúgbò rẹ ní òwúrọ̀
15 Àyà tí ó máa ń jà dàbí
16 dídá a lẹ́kun dàbí ìgbà tí ènìyàn ń dá afẹ́fẹ́ lẹ́kun
17 Bí irin tí ń pọ́n irin mú
18 Ẹni tí ó tọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́ yóò jẹ èso rẹ̀
19 Bí omi tí ń ṣe àfihàn ojú, nígbà tí a bá wò ó
20 Kò tẹ́ ikú àti ìparun lọ́rùn rí
21 Iná fún fàdákà iná ìléru fún wúrà,
22 Bí a tilẹ̀ gún aláìgbọ́n nínú odó,
23 Rí i dájú pé o mọ ipò tí àwọn agbo àgùntàn rẹ wà
24 nítorí ọrọ̀ kì í pẹ́ lọ títí
25 Nígbà tí a bá kó koríko, ewéko tuntun yóò sì hù jáde, a ó sì kó koríko àwọn orí òkè wọlé
26 àwọn àgùntàn yóò pèsè aṣọ fún ọ,
27 Ìwọ yóò ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàrà ewúrẹ́