1 Ọkàn ọba ń bẹ lọ́wọ́ Olúwa;
2 Gbogbo ọ̀nà ènìyàn dàbí i pé ó dára lójú rẹ̀,
3 Ṣíṣe ohun tí ó dára tí ó sì tọ̀nà
4 Ojú tí ó gbéga àti ọkàn ìgbéraga,
5 Ètè àwọn olóye jásí èrè
6 Ìṣúra tí a kójọ nípasẹ̀ ahọ́n tí ń parọ́
7 Ìwà ipá àwọn ènìyàn búburú yóò wọ́ wọn lọ,
8 Ọ̀nà ẹlẹ́ṣẹ̀ kún fún ìwà ẹ̀ṣẹ̀
9 Ó sàn láti máa gbé ní kọ̀rọ̀ orí òrùlé
10 Ènìyàn búburú ń fẹ́ ibi
11 Nígbà tí a bá ń fìyà jẹ ẹlẹ́gàn,
12 Olódodo ṣàkíyèsí ilé ènìyàn búburú
13 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ti di etí rẹ̀ sí igbe olùpọ́njú,
14 Ọ̀rẹ́ ìkọ̀kọ̀, mú ìbínú kúrò:
15 Ayọ̀ ni fún olódodo láti ṣe ìdájọ́:
16 Ẹni tí ó bá yà kúrò ní ọ̀nà òye,
17 Ẹni tí ó bá fẹ́ afẹ́, yóò di tálákà:
18 Ènìyàn búburú ni yóò ṣe owó ìràpadà fún olódodo,
19 Ó sàn láti jókòó ní aginjù ju pẹ̀lú
20 Ìṣúra iyebíye àti òróró wà ní ibùgbé ọlọ́gbọ́n;
21 Ẹni tí ó bá tẹ̀lé òdodo àti àánú yóò rí ìyè,
22 Ọlọ́gbọ́n gòkè odi ìlú àwọn alágbára,
23 Ẹnikẹ́ni tí ó bá pa ẹnu àti ahọ́n rẹ̀ mọ́,
24 Agbéraga àti alágídí ènìyàn ń gan orúkọ ara rẹ̀ nítorí ó ń hùwà nínú ìwà ìgbéraga rẹ̀,
25 Ẹlẹ́rìí èké yóò ṣègbé, àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ yóò parun láé;
26 Ó ń fi ìlara ṣe ojúkòkòrò ní gbogbo ọjọ́:
27 Ẹbọ ènìyàn búburú, ìríra ni:
28 Ẹlẹ́rìí èké yóò ṣègbé:
29 Ènìyàn búburú mú ojú ara rẹ̀ le:
30 Kò sí ọgbọ́n, kò sí ìmòye,
31 A ń múra ẹṣin sílẹ̀ de ọjọ́ ogun: