Provérbios 22

YOR

1 Yíyan orúkọ rere sàn ju púpọ̀ ọrọ̀ lọ,

2 Ọlọ́rọ̀ àti tálákà péjọpọ̀:

3 Ọlọ́gbọ́n ènìyàn ti rí ibi tẹ́lẹ̀,

4 Èrè ìrẹ̀lẹ̀ àti ìbẹ̀rù Olúwa ni ọrọ̀ ọlá, àti ìyè.

5 Ègún àti ìdẹ̀kùn ń bẹ ní ọ̀nà aláyídáyidà:

6 Tọ́ ọmọdé ní ọ̀nà tí yóò tọ̀:

7 Ọlọ́rọ̀ ṣe olórí olùpọ́njú,

8 Ẹni tí ó bá fúnrúgbìn ẹ̀ṣẹ̀, yóò ká asán:

9 Ẹni tí ó ní ojú àánú ni a ó bùkún fún;

10 Lé ẹlẹ́gàn sí ìta, ìjà yóò sì jáde;

11 Ẹni tí ó fẹ́ ìwà funfun ti àyà,

12 Ojú Olúwa pa ìmọ̀ mọ́,

13 Ọ̀lẹ wí pé, “Kìnnìún ń bẹ lóde!

14 Ẹnu àwọn àjèjì obìnrin, ihò jíjìn ni;

15 Àyà ọmọdé ni ìwà wèrè dì sí;

16 Ẹni tó ń ni tálákà lára láti ní ọrọ̀,

17 Dẹtí rẹ sílẹ̀,

18 Nítorí ohun dídùn ni bí ìwọ bá pa wọ́n mọ́ ní inú rẹ;

19 Kí ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ lè wà ní ti Olúwa,

20 Èmi kò ha ti kọ̀wé ohun dáradára

21 kí ó lè mú ọ mọ ìdájú ọ̀rọ̀ òtítọ́;

22 Má ṣe ja tálákà ní olè, nítorí tí ó jẹ́ tálákà:

23 nítorí Olúwa yóò gbèjà wọn,

24 Má ṣe bá oníbìínú ènìyàn ṣe ọ̀rẹ́;

25 Kí ìwọ má ba à kọ́ ìwà rẹ̀, ìwọ a sì gba ìkẹ́kùn fún ara rẹ.

26 Má ṣe wà nínú àwọn tí ń ṣe ìgbọ̀nwọ́,

27 Bí ìwọ kò bá ní nǹkan tí ìwọ ó fi san,

28 Má ṣe yẹ ààlà ilẹ̀ ìgbàanì,

29 Ìwọ ha rí ènìyàn tí ó ń fi àìṣe ìmẹ́lẹ́ ṣe iṣẹ́ rẹ̀?

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado