Provérbios 20

YOR

1 Ẹlẹ́yà ni ọtí wáìnì, aláriwo sì ní ọtí líle;

2 Ìbẹ̀rù ọba dàbí kíké e kìnnìún;

3 Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti sá fún ìjà,

4 Ọ̀lẹ kì í ṣiṣẹ́ oko nígbà tí ó yẹ,

5 Ète ọkàn ènìyàn dàbí omi jíjìn;

6 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n máa ń sọ pe àwọn ní ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn,

7 Olódodo ènìyàn a máa gbé ìgbé ayé àìlábùkù

8 Nígbà tí ọba bá jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀ láti ṣe ìdájọ́

9 Ta ni ó le è wí pé, “Mo ti ṣe ọkàn mi ní mímọ́,

10 Ìwọ̀n èké àti òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ

11 Kódà a mọ ọmọdé nípa iṣẹ́ rẹ̀

12 Etí tí ó ń gbọ́ àti ojú tí ó ń ríran

13 Má ṣe fẹ́ràn oorun, àìṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ yóò di tálákà.

14 “Kò dára, kò dára!” ní ẹni tó ra ọjà máa ń wí;

15 Wúrà wà, iyùn sì wà rẹpẹtẹ,

16 Gba abọ́ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àlejò;

17 Oúnjẹ tí a fi ọ̀nà èrú rí máa ń dùn lẹ́nu ènìyàn,

18 Pa ètè rẹ mọ́ nípa wíwá ìmọ̀ràn

19 Olófòófó a máa tú àṣírí

20 Bí ènìyàn kan bá ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀,

21 Ogún tí a kójọ kíákíá ní ìbẹ̀rẹ̀

22 Má ṣe wí pé, “N ó sẹ̀san àṣìṣe rẹ yìí fún ọ.”

23 Olúwa kórìíra òdínwọ̀n èké.

24 Olúwa ni ó ń ṣe olùdarí ìgbésẹ̀ ènìyàn.

25 Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá

26 Ọlọ́gbọ́n ọba tú ènìyàn búburú ká;

27 Àtùpà Olúwa ń ṣe àwárí ẹ̀mí ènìyàn

28 Ìfẹ́ àti òdodo pa ọba mọ́,

29 Ògo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ni agbára wọn,

30 Ìgbájú ìgbámú àti ìfarapa máa ń mú ibi lọ,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado