1 Ó sàn kí ènìyàn jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ kò lábùkù
2 Kò dára láti ní ìtara láìní ìmọ̀,
3 Ìwà òmùgọ̀ ènìyàn fúnra rẹ̀ a pa ẹ̀mí rẹ̀ run;
4 Ọrọ̀ máa ń fa ọ̀rẹ́ púpọ̀;
5 Ajẹ́rìí èké kò ní lọ láìjìyà,
6 Ọ̀pọ̀ ń wá ojúrere olórí;
7 Gbogbo ará ilé e tálákà ni ó pa á tì,
8 Ẹni tí ó gba ọgbọ́n fẹ́ràn ọkàn ara rẹ̀;
9 Ajẹ́rìí èké kì yóò lọ láìjìyà
10 Kò yẹ aláìgbọ́n láti máa gbé nínú ọláńlá,
11 Ọgbọ́n ènìyàn a máa fún un ní sùúrù;
12 Ìbínú ọba dàbí kíké e kìnnìún,
13 Aṣiwèrè ọmọ jẹ́ ìparun baba rẹ̀,
14 A máa ń jogún ilé àti ọrọ̀ lọ́dọ̀ òbí,
15 Ọ̀lẹ ṣíṣe máa ń fa oorun sísùn fọnfọn,
16 Ẹnikẹ́ni tí ó gbọ́ ẹ̀kọ́ pa ẹnu rẹ̀ mọ́,
17 Ẹni tí ó ṣàánú tálákà, Olúwa ní ó yá,
18 Bá ọmọ rẹ wí nítorí nínú ìyẹn ni ìrètí wà;
19 Ènìyàn onínú-fùfù gbọdọ̀ gba èrè ìwà rẹ̀;
20 Fetí sí ìmọ̀ràn kí o sì gba ẹ̀kọ́,
21 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn,
22 Ohun tí ènìyàn ń fẹ́ ni ìfẹ́ tí kì í yẹ̀;
23 Ìbẹ̀rù Olúwa ń mú ìyè wá;
24 Ọ̀lẹ ki ọwọ́ rẹ̀ bọ inú àwo oúnjẹ;
25 Na ẹlẹ́gàn, òpè yóò sì kọ́gbọ́n;
26 Ẹni tí ó ṣìkà sí baba rẹ̀, tí ó sì lé ìyá rẹ̀ jáde
27 Ọmọ mi, dẹ́kun láti tẹ́tí sí ẹ̀kọ́,
28 Ẹlẹ́rìí búburú fi ìdájọ́ ṣẹ̀sín,
29 A ti pèsè ìjìyà sílẹ̀ fún ẹlẹ́gàn;