Provérbios 18

YOR

1 Ènìyàn tí kò ba ni rẹ́ a máa lépa ìmọ̀ ara rẹ̀;

2 Aláìgbọ́n kò rí inú dídùn sí òye

3 Nígbà ti ènìyàn búburú dé ni ẹ̀gàn dé,

4 Ọ̀rọ̀ ẹnu ènìyàn jẹ́ omi jíjìn,

5 Kò dára kí ènìyàn ṣe ojúsàájú fún ènìyàn búburú

6 Ètè aláìgbọ́n dá ìjà sílẹ̀

7 Ẹnu aláìgbọ́n ni ó ba tirẹ̀ jẹ́,

8 Ọ̀rọ̀ olófòófó dàbí oúnjẹ àdídùn;

9 Ẹni tí kò ṣe déédé nínú iṣẹ́ rẹ̀

10 Orúkọ Olúwa, ilé ìṣọ́ agbára ni;

11 Ọ̀rọ̀ olówó ni ìlú olódi wọn;

12 Ṣáájú ìṣubú ọkàn ènìyàn a kọ́kọ́ máa gbéraga,

13 Ẹni tí ó ń fèsì kí ó tó gbọ́,

14 Ọkàn ènìyàn a máa gbé e ró nígbà àìsàn,

15 Ọkàn olóye ní i gba ìmọ̀;

16 Ẹ̀bùn máa ń ṣí ọ̀nà fún ẹni tí ń fún ni lẹ́bùn

17 Ẹni tí ó kọ́kọ́ rọjọ́ máa ń dàbí i pé ó jàre,

18 Ìbò dídì máa ń parí ìjà

19 Arákùnrin tí a ṣẹ̀ sí ṣòro yípadà ju ìlú olódi lọ,

20 Láti inú èso ẹnu rẹ̀ ikùn ènìyàn a yó;

21 Ikú àti ìyè ń bẹ nípa ahọ́n wọn,

22 Ẹni tí ó rí aya fẹ́, rí ohun rere,

23 Tálákà ń bẹ̀bẹ̀ fún àánú,

24 Ènìyàn tí ó ní ọ̀rẹ́ púpọ̀ le è parun,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado