Provérbios 14

YOR

1 Ọlọ́gbọ́n obìnrin kọ́ ilé e rẹ̀,

2 Ẹni tí ń rìn déédé bẹ̀rù Olúwa,

3 Ọ̀rọ̀ aṣiwèrè a máa ṣokùnfà pàṣán fún ẹ̀yìn rẹ̀,

4 Níbi tí kò sí ẹran, ibùjẹ ẹran a máa mọ́ tónítóní,

5 Ẹlẹ́rìí tí ń ṣọ òtítọ́ kì í tan ni

6 Ẹlẹ́gàn ń wá ọgbọ́n kò sì rí rárá,

7 Má ṣe súnmọ́ aláìgbọ́n ènìyàn,

8 Ọgbọ́n olóye ni láti ronú jinlẹ̀ nípa ọ̀nà wọn

9 Aláìgbọ́n ń dẹ́ṣẹ̀ nígbà tí ó yẹ kí ó ṣe àtúnṣe ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀

10 Ọkàn kọ̀ọ̀kan ló mọ ẹ̀dùn ọkàn tirẹ̀

11 A ó pa ilé ènìyàn búburú run,

12 Ọ̀nà kan wà tí ó dàbí i pé ó dára lójú ènìyàn,

13 Kódà nígbà tí a ń rẹ́rìn-ín, ọkàn le è máa kérora;

14 A ó san án lẹ́kùnrẹ́rẹ́ fún aláìgbàgbọ́ gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀,

15 Òpè ènìyàn gba ohun gbogbo gbọ́

16 Ọlọ́gbọ́n bẹ̀rù Ọlọ́run ó sì kórìíra ibi

17 Ẹni tí ó máa ń tètè bínú máa ń hùwà aṣiwèrè,

18 Òpè jogún ìwà òmùgọ̀

19 Ènìyàn ìkà yóò tẹríba níwájú àwọn ènìyàn rere

20 Kódà àwọn aládùúgbò tálákà kò fẹ́ràn rẹ̀,

21 Ẹni tí ó kẹ́gàn aládùúgbò o rẹ̀ ti dẹ́ṣẹ̀

22 Ǹjẹ́ àwọn tí ń pète ibi kì í ṣìnà bí?

23 Gbogbo iṣẹ́ àṣekára ló máa ń mú èrè wá,

24 Ọrọ̀ ọlọ́gbọ́n ènìyàn ni adé orí wọn

25 Ẹlẹ́rìí tí ó ṣọ òtítọ́ gba ẹ̀mí là

26 Nínú ìbẹ̀rù Olúwa ni ìgbẹ́kẹ̀lé tí ó lágbára,

27 Ìbẹ̀rù Olúwa jẹ́ orísun ìyè,

28 Ènìyàn púpọ̀ ní ìlú jẹ́ ògo ọba,

29 Onísùúrù ènìyàn ní òye tí ó pọ̀,

30 Ọkàn tí ó lálàáfíà fi ìyè mú kí ọjọ́ ayé gùn fún ara,

31 Ẹni tí ó fi ìyà jẹ aláìní ń fi ìkórìíra hàn

32 Nígbà tí ìyọnu bá dé, a fa àwọn búburú lulẹ̀,

33 Ọgbọ́n wà nínú ọkàn olóye

34 Òdodo a máa gbé orílẹ̀-èdè lékè,

35 Ọba a máa ní inú dídùn sí ìránṣẹ́ tí ó gbọ́n

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado