1 Má ṣe yọ̀, ìwọ Israẹli;
2 Àwọn ilẹ̀ ìpakà àti ilé ìfun wáìnì kò ní fún àwọn ènìyàn lóúnjẹ
3 Wọn kò ní ṣẹ́kù sí ilé Olúwa
4 Wọn kò ní fi ọrẹ ohun mímu fún Olúwa.
5 Kí ni ẹ̀yin ó ṣe ní ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn
6 Bí wọ́n tilẹ̀ yọ́ kúrò lọ́wọ́ ìparun
7 Àwọn ọjọ́ ìjìyà ń bọ̀;
8 Wòlíì, papọ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run,
9 Wọ́n ti gbilẹ̀ nínú ìwà ìbàjẹ́
10 “Mo rí Israẹli bí èso àjàrà ní aginjù.
11 Ògo Efraimu yóò fò lọ bí ẹyẹ
12 Bí wọ́n tilẹ̀ tọ́ ọmọ dàgbà.
13 Mo rí Efraimu bí ìlú Tire
14 Fún wọn, Olúwa!
15 “Nítorí gbogbo ìwà búburú tí wọ́n hù ní Gilgali,
16 Efraimu ti rẹ̀ dànù
17 Ọlọ́run mi yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀