1 “Fi ìpè sí ẹnu rẹ!
2 Israẹli kígbe pè mí,
3 Ṣùgbọ́n Israẹli ti kọ ohun tí ó dára sílẹ̀
4 Wọ́n fi àwọn ọba jẹ ṣùgbọ́n, kì í ṣe nípasẹ̀ mi
5 Ju ère ẹgbọrọ màlúù rẹ, ìwọ Samaria!
6 Israẹli ni wọ́n ti wá!
7 “Wọ́n gbin afẹ́fẹ́
8 A ti gbé Israẹli mì,
9 Nítorí pé wọ́n ti gòkè lọ sí Asiria
10 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti ta ara wọn sí àárín Orílẹ̀-èdè,
11 “Nítorí Efraimu ti kọ́ pẹpẹ púpọ̀ fún ìrúbọ ẹ̀ṣẹ̀
12 Mo kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun tí ó jẹ́ òfin mi fún wọn,
13 Wọ́n ń rú ẹbọ tí wọ́n yàn fún mi,
14 Nítorí Israẹli ti gbàgbé ẹlẹ́dàá rẹ̀