1 Israẹli jẹ́ igi àjàrà tó gbilẹ̀
2 Ọkàn wọn kún fún ìtànjẹ
3 Nígbà náà ni wọn yóò wí pé, “A kò ní ọba
4 Wọ́n ṣe ìlérí púpọ̀,
5 Àwọn ènìyàn tí ń gbé Samaria bẹ̀rù
6 A ó gbé lọ sí Asiria
7 Bí igi tó léfòó lórí omi ni
8 Àwọn ibi gíga tí ẹ tí ń hùwà búburú ni a o parun,
9 “Láti ìgbà Gibeah, ni ó ti ṣẹ̀, ìwọ Israẹli,
10 Nígbà tó bá tẹ́ mi lọ́rùn, èmi yóò fi ìyà jẹ wọ́n;
11 Efraimu jẹ́ ọmọ abo màlúù tí a tí kọ́,
12 Ẹ gbin òdòdó fún ara yín,
13 Ṣùgbọ́n ẹ tí gbin búburú ẹ si ka ibi,
14 ariwo ogun yóò bo àwọn ènìyàn yín
15 Báyìí ni a o sì ṣe sí ọ, ìwọ Beteli,