1 Yípadà ìwọ Israẹli sí Olúwa Ọlọ́run rẹ.
2 Ẹ gba ọ̀rọ̀ Olúwa gbọ́,
3 Asiria kò le gbà wá là;
4 “Èmi wo àgàbàgebè wọn sàn,
5 Èmi o dàbí ìrì sí Israẹli,
6 Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ ẹ̀ka rẹ̀ yóò dàgbà,
7 Àwọn ènìyàn yóò tún padà gbé lábẹ́ òjijì rẹ̀.
8 Ìwọ Efraimu, kín ló tún kù tí mo ní ṣe pẹ̀lú ère òrìṣà?
9 Ta ni ọlọ́gbọ́n? Òun yóò mòye àwọn nǹkan wọ̀nyí.