1 Nígbà ti Efraimu bá ń sọ̀rọ̀, àwọn ènìyàn máa ń wárìrì,
2 Báyìí, wọ́n ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀;
3 Nítorí náà wọn yóò dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀,
4 “Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀,
5 Mo ṣe ìtọ́jú rẹ ní aginjù,
6 Wọn ni ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí mo fún wọn ní oúnjẹ,
7 Nítorí náà, Èmi yóò dìde sí wọn bí i kìnnìún,
8 Beari igbó tí a já ọmọ rẹ̀ gbà,
9 “A ti pa ọ́ run, ìwọ Israẹli,
10 Níbo ni ọba rẹ gbé wà nísinsin yìí kí ó bá à le gbà ọ là?
11 Nítorí èyí nínú ìbínú mi ni mo fún un yín ní ọba,
12 Ẹ̀bi Efraimu ni a tí ko jọ
13 Ìrora bí obìnrin tó fẹ́ bímọ ti dé bá a,
14 “Èmi yóò rà wọ́n padà kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú.
15 Bí ó tilẹ̀ gbilẹ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀
16 Ará Samaria gbọdọ̀ ru ẹ̀bi wọn,