Oséias 12

YOR

1 Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;

2 Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,

3 Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,

4 Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀,

5 àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;

6 Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;

7 Oníṣòwò ń lo òsùwọ̀n èké

8 Efraimu gbéraga,

9 “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;

10 Mo sọ fún àwọn wòlíì,

11 Gileadi ha burú bí?

12 Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;

13 Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,

14 Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado