1 Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;
2 Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,
3 Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,
4 Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀,
5 àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;
6 Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;
7 Oníṣòwò ń lo òsùwọ̀n èké
8 Efraimu gbéraga,
9 “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;
10 Mo sọ fún àwọn wòlíì,
11 Gileadi ha burú bí?
12 Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;
13 Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,
14 Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;