Naum 3

YOR

1 Ègbé ni fún ìlú ẹ̀jẹ̀ nì,

2 Ariwo pàṣán àti ariwo

3 Ológun orí ẹṣin ń fi ìgbónára

4 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ panṣágà

5 “Èmi dojúkọ ọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.

6 Èmi yóò da ẹ̀gbin tí ó ni ìríra sí ọ ní ara,

7 Gbogbo àwọn tí ó ba sì wò ọ́ yóò sì káàánú fún ọ, wọn yóò sì wí pé,

8 Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Tebesi lọ,

9 Etiopia àti Ejibiti ni agbára rẹ, kò sí ní òpin;

10 Síbẹ̀síbẹ̀ a kó o ní ìgbèkùn

11 Ìwọ pẹ̀lú yóò sì mu àmupara;

12 Gbogbo ilé ìṣọ́ agbára rẹ yóò dàbí igi ọ̀pọ̀tọ́

13 Kíyèsi gbogbo àwọn jagunjagun!

14 Pọn omi nítorí ìhámọ́,

15 Níbẹ̀ ni iná yóò ti jó ọ́ run;

16 Ìwọ ti sọ àwọn oníṣòwò rẹ di púpọ̀

17 Àwọn aládé rẹ̀ dàbí eṣú,

18 Ìwọ ọba Asiria,

19 Kò sì sí ohun tí ó lè wo ọgbẹ́ ẹ̀ rẹ sàn;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado