1 Ègbé ni fún ìlú ẹ̀jẹ̀ nì,
2 Ariwo pàṣán àti ariwo
3 Ológun orí ẹṣin ń fi ìgbónára
4 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ panṣágà
5 “Èmi dojúkọ ọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
6 Èmi yóò da ẹ̀gbin tí ó ni ìríra sí ọ ní ara,
7 Gbogbo àwọn tí ó ba sì wò ọ́ yóò sì káàánú fún ọ, wọn yóò sì wí pé,
8 Ǹjẹ́ ìwọ ha sàn ju Tebesi lọ,
9 Etiopia àti Ejibiti ni agbára rẹ, kò sí ní òpin;
10 Síbẹ̀síbẹ̀ a kó o ní ìgbèkùn
11 Ìwọ pẹ̀lú yóò sì mu àmupara;
12 Gbogbo ilé ìṣọ́ agbára rẹ yóò dàbí igi ọ̀pọ̀tọ́
13 Kíyèsi gbogbo àwọn jagunjagun!
14 Pọn omi nítorí ìhámọ́,
15 Níbẹ̀ ni iná yóò ti jó ọ́ run;
16 Ìwọ ti sọ àwọn oníṣòwò rẹ di púpọ̀
17 Àwọn aládé rẹ̀ dàbí eṣú,
18 Ìwọ ọba Asiria,
19 Kò sì sí ohun tí ó lè wo ọgbẹ́ ẹ̀ rẹ sàn;