1 Àwọn apanirun ti dìde sí ọ, ìwọ Ninefe.
2 Olúwa yóò mú ọláńlá Jakọbu padà sípò
3 Asà àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ sì di pupa;
4 Àwọn kẹ̀kẹ́ ogun yóò ya bo àwọn pópónà,
5 Ninefe yóò ṣe àṣàrò àwọn ọlọ́lá rẹ̀;
6 A ó ṣí ìlẹ̀kùn àwọn odò wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀,
7 A pa á láṣẹ pé ìlú náà, èyí tí a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀
8 Ninefe dàbí adágún omi,
9 “Ẹ kó ìkógun fàdákà!
10 Òun ti ṣòfò, ó si di asán, ó sì di ahoro:
11 Níbo ni ihò àwọn kìnnìún wà
12 Kìnnìún tipa ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀,
13 “Kíyèsi i èmi dojúkọ ọ́,”