1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.
2 Ọlọ́run ń jẹ owú, ó sì ń gbẹ̀san,
3 Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì tóbi ní agbára;
4 Ó bá òkun wí, ó sì mú kí ó gbẹ;
5 Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀,
6 Ta ni ó lé dúró níwájú ìbínú rẹ̀?
7 Rere ni Olúwa,
8 ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìkún omi ńlá
9 Kí ni ẹ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì sí Olúwa?
10 Wọn yóò sì lọ́lù papọ̀ bí ẹ̀gún òṣùṣú
11 Láti ọ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde wá
12 Báyìí ni Olúwa wí:
13 Nísinsin yìí ni èmi yóò já àjàgà wọn kúrò ní ọrùn rẹ
14 Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe:
15 Wò ó, lórí àwọn òkè,