1 Nísinsin yìí, kó àwọn ọ̀wọ́ ogun rẹ jọ,
2 “Ṣùgbọ́n ìwọ, Bẹtilẹhẹmu Efrata,
3 Nítorí náà Israẹli yóò di kíkọ̀sílẹ̀ pátápátá
4 Òun yóò sì dúró,
5 Òun yóò sì jẹ́ àlàáfíà wọn.
6 Wọn yóò sì fi idà pa ilẹ̀ Asiria run,
7 Ìyókù Jakọbu yóò sì wà
8 Ìyókù Jakọbu yóò sì wà láàrín àwọn aláìkọlà
9 A ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀,
10 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí,
11 Èmi yóò sì pa ilẹ̀ ìlú ńlá rẹ̀ run,
12 Èmi yóò gé ìwà àjẹ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ̀,
13 Èmi yóò pa àwọn ère fínfín rẹ̀ run,
14 Èmi yóò fa ère Aṣerah tu kúrò láàrín rẹ̀,
15 Èmi yóò gbẹ̀san ní ìbínú àti ìrunú