1 Ní ọjọ́ ìkẹyìn
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò wá,
3 Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn,
4 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yóò jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀
5 Gbogbo àwọn ènìyàn ń rìn,
6 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí,
7 Èmi yóò dá àwọn arọ sí fún èyí tókù,
8 Ní ti ìwọ, ilé ìṣọ́ agbo àgùntàn,
9 Kí ni ìwọ ha ń kígbe sókè sí nísinsin yìí?
10 Máa yí síyìn-ín sọ́hùn-ún nínú ìrora,
11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ Orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọ sí ọ.
12 Ṣùgbọ́n wọn kò mọ
13 “Dìde, kí ó sì máa pa ọkà ìwọ ọmọbìnrin Sioni,