1 Nígbà náà, ni mo wí pé,
2 Ẹ̀yin tí ó kórìíra ìre, tí ẹ sì fẹ́ràn ibi;
3 àwọn tí ó jẹ ẹran-ara àwọn ènìyàn mi,
4 Nígbà náà ni wọn yóò kígbe sí Olúwa,
5 Báyìí ni Olúwa wí,
6 Nítorí náà òru yóò wá sórí yín,
7 Ojú yóò sì ti àwọn wòlíì
8 Ṣùgbọ́n ní tèmi,
9 Gbọ́ ẹ̀yin olórí ilé Jakọbu,
10 tí ó kọ́ Sioni pẹ̀lú ìtàjẹ̀ sílẹ̀,
11 Àwọn olórí rẹ̀ ń ṣe ìdájọ́ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,
12 Nítorí náà, nítorí tiyín,