1 Ègbé ni fún àwọn tí ń gbèrò àìṣedéédéé
2 Wọ́n sì ń ṣe ojúkòkòrò oko, wọ́n sì fi agbára wọn gbà wọ́n,
3 Nítorí náà, Olúwa wí pé:
4 Ní ọjọ́ náà ni ẹnìkan yóò pa òwe kan sí yín;
5 Nítorí náà, ìwọ kò ní ní ẹnìkankan tí yóò ta okùn nínú ìjọ Olúwa,
6 “Ẹ má ṣe sọtẹ́lẹ̀,” ni àwọn wòlíì wọn wí.
7 Ṣé kí á sọ ọ́, ìwọ ilé Jakọbu:
8 Láìpẹ́ àwọn ènìyàn mi dìde
9 Ẹ̀yin sì lé obìnrin àwọn ènìyàn mi
10 Ẹ dìde, kí ẹ sì máa lọ!
11 Tí òpùrọ́ àti ẹlẹ́tàn bá wà tí wọ́n sì wí pé,
12 “Èmi yóò kó gbogbo yín jọ, ìwọ Jakọbu;
13 Ẹni tí ó ń fọ ọ̀nà yóò lọ sókè níwájú wọn;