1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Mika ará Moreṣeti wá ní àkókò ìjọba Jotamu, Ahasi, àti Hesekiah, àwọn ọba Juda nìwọ̀nyí, ìran tí ó rí nípa Samaria àti Jerusalẹmu.
2 Ẹ gbọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn,
3 Wò ó! Olúwa ń bọ̀ wá láti ibùgbé rẹ̀;
4 Àwọn òkè ńlá yóò sí yọ́ lábẹ́ rẹ̀,
5 Nítorí ìré-òfin-kọjá Jakọbu ni gbogbo èyí,
6 “Nítorí náà, èmi yóò ṣe Samaria bí òkìtì lórí pápá,
7 Gbogbo àwọn ère fínfín rẹ̀ ni a ó fọ́ sí wẹ́wẹ́
8 Nítorí èyí, èmi yóò sì sọkún,
9 Nítorí tí ọgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláìlèwòtán;
10 Ẹ má ṣe sọ ní Gati
11 Ẹ kọjá lọ ni ìhòhò àti ni ìtìjú,
12 Nítorí àwọn tí ó ń gbé ni Marati ń retí ìre,
13 Ìwọ olùgbé Lakiṣi,
14 Nítorí náà ni ìwọ ó ṣe fi ìwé ìkọ̀sílẹ̀
15 Èmi yóò sì mú àrólé kan wá sórí rẹ ìwọ olùgbé Meraṣa.
16 Fá irun orí rẹ nínú ọ̀fọ̀