1 Báwo ni wúrà ṣe sọ ògo dídán rẹ̀ nù,
2 Báwo ni àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Sioni tí ó ṣe iyebíye,
3 Àwọn ajáko pèsè ọmú wọn
4 Nítorí òǹgbẹ, ahọ́n àwọn ọmọ ọwọ́
5 Àwọn tí ó ń jẹ ohun dáradára
6 Ìjìyà àwọn ènìyàn mi
7 Ọmọ ọba ọkùnrin wọn mọ́ ju òjò-dídì,
8 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n dúdú ju èédú;
9 Àwọn tí ó kù nípasẹ̀ idà sàn
10 Pẹ̀lú ọwọ́ àwọn obìnrin aláàánú
11 Olúwa ti fi ihò kíkún fún ìbínú rẹ̀;
12 Àwọn ọba ayé kò gbàgbọ́,
13 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn wòlíì
14 Nísinsin yìí wọ́n ń rìn kiri ní òpópó
15 “Lọ kúrò! Ẹ̀yin di aláìmọ́!” ni àwọn ènìyàn ń kígbe sí wọn.
16 Olúwa ti tú wọn ká fúnra rẹ̀;
17 Síwájú sí i, ojú wa kùnà
18 Wọ́n ń ṣọ́ wa kiri,
19 Àwọn tí ń lé wa yára
20 Ẹni àmì òróró Olúwa, èémí ìyè wa,
21 Ẹ yọ̀ kí inú yín sì dùn, ẹ̀yin ọmọbìnrin Edomu,
22 Ìwọ ọmọbìnrin Sioni, ìjìyà rẹ yóò dópin;