Lamentações 4

YOR

1 Báwo ni wúrà ṣe sọ ògo dídán rẹ̀ nù,

2 Báwo ni àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Sioni tí ó ṣe iyebíye,

3 Àwọn ajáko pèsè ọmú wọn

4 Nítorí òǹgbẹ, ahọ́n àwọn ọmọ ọwọ́

5 Àwọn tí ó ń jẹ ohun dáradára

6 Ìjìyà àwọn ènìyàn mi

7 Ọmọ ọba ọkùnrin wọn mọ́ ju òjò-dídì,

8 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n dúdú ju èédú;

9 Àwọn tí ó kù nípasẹ̀ idà sàn

10 Pẹ̀lú ọwọ́ àwọn obìnrin aláàánú

11 Olúwa ti fi ihò kíkún fún ìbínú rẹ̀;

12 Àwọn ọba ayé kò gbàgbọ́,

13 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn wòlíì

14 Nísinsin yìí wọ́n ń rìn kiri ní òpópó

15 “Lọ kúrò! Ẹ̀yin di aláìmọ́!” ni àwọn ènìyàn ń kígbe sí wọn.

16 Olúwa ti tú wọn ká fúnra rẹ̀;

17 Síwájú sí i, ojú wa kùnà

18 Wọ́n ń ṣọ́ wa kiri,

19 Àwọn tí ń lé wa yára

20 Ẹni àmì òróró Olúwa, èémí ìyè wa,

21 Ẹ yọ̀ kí inú yín sì dùn, ẹ̀yin ọmọbìnrin Edomu,

22 Ìwọ ọmọbìnrin Sioni, ìjìyà rẹ yóò dópin;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado