Lamentações 5

YOR

1 Rántí, Olúwa, ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wa;

2 Àwọn ohun ìní wa ti di ti àlejò,

3 Àwa ti di aláìní òbí àti aláìní baba,

4 A gbọdọ̀ ra omi tí à ń mu;

5 Àwọn tí ó ń lé wa súnmọ́ wa;

6 Àwa jọ̀wọ́ ara wa fún Ejibiti àti Asiria

7 Àwọn baba wa ti ṣẹ̀, wọn kò sì ṣí mọ́,

8 Àwọn ẹrú ń jẹ ọba lórí wa,

9 Àwa ń rí oúnjẹ wa nínú ewu ẹ̀mí wa

10 Ẹran-ara wa gbóná bí ààrò,

11 Wọ́n ti fipá bá àwọn obìnrin wa lòpọ̀ ní Sioni,

12 Àwọn ọmọ ọbakùnrin ti di síso sókè ní ọwọ́ wọn;

13 Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wa ru òkúta;

14 Àwọn àgbàgbà ti lọ kúrò ní ẹnu-bodè ìlú;

15 Ayọ̀ ti ṣáko ní ọkàn wa;

16 Adé ti ṣí kúrò ní orí wa

17 Nítorí èyí, àárẹ̀ mú ọkàn wa,

18 Fún òkè Sioni tí ó ti di ahoro

19 Ìwọ, Olúwa, jẹ ọba títí láé;

20 Kí ló dé tí o ń gbàgbé wa ní gbogbo ìgbà?

21 Mú wa padà sí ọ̀dọ̀ rẹ, Olúwa, kí àwa kí ó le padà;

22 àyàfi tí o bá ti kọ̀ wá sílẹ̀ pátápátá

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado