1 Rántí, Olúwa, ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wa;
2 Àwọn ohun ìní wa ti di ti àlejò,
3 Àwa ti di aláìní òbí àti aláìní baba,
4 A gbọdọ̀ ra omi tí à ń mu;
5 Àwọn tí ó ń lé wa súnmọ́ wa;
6 Àwa jọ̀wọ́ ara wa fún Ejibiti àti Asiria
7 Àwọn baba wa ti ṣẹ̀, wọn kò sì ṣí mọ́,
8 Àwọn ẹrú ń jẹ ọba lórí wa,
9 Àwa ń rí oúnjẹ wa nínú ewu ẹ̀mí wa
10 Ẹran-ara wa gbóná bí ààrò,
11 Wọ́n ti fipá bá àwọn obìnrin wa lòpọ̀ ní Sioni,
12 Àwọn ọmọ ọbakùnrin ti di síso sókè ní ọwọ́ wọn;
13 Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wa ru òkúta;
14 Àwọn àgbàgbà ti lọ kúrò ní ẹnu-bodè ìlú;
15 Ayọ̀ ti ṣáko ní ọkàn wa;
16 Adé ti ṣí kúrò ní orí wa
17 Nítorí èyí, àárẹ̀ mú ọkàn wa,
18 Fún òkè Sioni tí ó ti di ahoro
19 Ìwọ, Olúwa, jẹ ọba títí láé;
20 Kí ló dé tí o ń gbàgbé wa ní gbogbo ìgbà?
21 Mú wa padà sí ọ̀dọ̀ rẹ, Olúwa, kí àwa kí ó le padà;
22 àyàfi tí o bá ti kọ̀ wá sílẹ̀ pátápátá