1 Báwo ni Olúwa ṣe bo ọmọbìnrin Sioni
2 Láìní àánú ni Olúwa gbé
3 Ní ìbínú gbígbóná rẹ̀ ni ó ké
4 Ó na ọfà rẹ̀ bí ọ̀tá;
5 Olúwa dàbí ọ̀tá;
6 Ó mú ìparun bá ibi mímọ́,
7 Olúwa ti kọ̀ pẹpẹ rẹ̀ sílẹ̀
8 Olúwa pinnu láti fa
9 Ẹnu-ọ̀nà rẹ̀ ti wọ inú ilẹ̀;
10 Àwọn àgbàgbà ọmọbìnrin Sioni
11 Ojú mi kọ̀ láti sọkún,
12 Wọ́n wí fún àwọn ìyá wọn,
13 Kí ni mo le sọ fún ọ?
14 Ìran àwọn wòlíì rẹ
15 Àwọn tí ó gba ọ̀nà ọ̀dọ̀ rẹ
16 Gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ la ẹnu wọn
17 Olúwa ti ṣe ohun tí ó pinnu;
18 Ọkàn àwọn ènìyàn
19 Dìde, kígbe sókè ní àṣálẹ́,
20 “Wò ó, Olúwa, kí o sì rò ó.
21 “Ọmọdé àti àgbà ń sùn papọ̀
22 “Bí ó ti ṣe ní ọjọ́ àsè,