1 Báwo ni ìlú ṣe jókòó nìkan,
2 Ọ̀gànjọ́ òru ni ó fi máa ń sọkún kíkorò
3 Lẹ́yìn ìjìyà àti ìpọ́njú nínú oko ẹrú,
4 Gbogbo ọ̀nà tí ó wọ Sioni ń ṣọ̀fọ̀,
5 Àwọn aninilára rẹ̀ gbogbo di olúwa rẹ̀,
6 Gbogbo ẹwà ti di ohun ìgbàgbé
7 Ní ọjọ́ ìpọ́njú àti àrìnká rẹ̀ ni
8 Jerusalẹmu sì ti dẹ́ṣẹ̀ púpọ̀
9 Ìdọ̀tí wà ní etí aṣọ rẹ̀,
10 Ọ̀tá ti gbọ́wọ́ lé
11 Àwọn ènìyàn rẹ̀ ń kérora
12 “Kò ha jẹ́ nǹkan kan sí i yín?
13 “Ó rán iná láti òkè
14 “Ẹ̀ṣẹ̀ mi ti di sísopọ̀ sí àjàgà;
15 “Olúwa kọ
16 “Ìdí nìyí tí mo fi ń sọkún
17 Sioni na ọwọ́ jáde,
18 “Olóòtítọ́ ni Olúwa,
19 “Mo pe àwọn ọ̀rẹ́ mi
20 “Olúwa, wò ó, bí mo ti wà nínú ìnira!
21 “Àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìrora mi,
22 “Jẹ́ kí ìwà ìkà wọn wá síwájú rẹ;