1 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tó tọ wòlíì Jeremiah wá nípa àwọn Filistini, kí ó tó di pé Farao dojúkọ Gasa.
2 Báyìí ni Olúwa wí:
3 nígbà tí wọ́n bá gbọ́ ìró títẹ̀lé pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin alágbára
4 Nítorí tí ọjọ́ náà ti pé
5 Gasa yóò fá irun orí rẹ̀ nínú ọ̀fọ̀.
6 “Ẹ̀yin kígbe, ‘Yé è, idà Olúwa,
7 Ṣùgbọ́n báwo ni yóò ṣe sinmi,