Jeremias 46

YOR

1 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa àwọn Orílẹ̀-èdè.

2 Nípa Ejibiti.

3 “Ẹ múra àpáta, èyí tí ó tóbi, àti èyí tí ó kéré,

4 Ẹ di ẹṣin ní gàárì,

5 Kí ni nǹkan tí mo tún rí?

6 “Ẹni tí ó yára kì yóò le sálọ,

7 “Ta ni èyí tí ó gòkè wá bí odò Ejibiti,

8 Ejibiti dìde bí odò náà,

9 Ẹ gòkè wá ẹ̀yin ẹṣin,

10 Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà jẹ́ ti Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

11 “Gòkè lọ sí Gileadi, kí o sì mú ìkunra,

12 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ nípa ìtìjú rẹ,

13 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó bá Jeremiah wòlíì nì sọ nípa wíwá Nebukadnessari ọba Babeli láti lọ dojú ìjà kọ Ejibiti:

14 “Kéde èyí ní Ejibiti, sì sọ ọ́ ní Migdoli,

15 Èéṣe tí àwọn akọni rẹ fi ṣubú?

16 Wọn yóò máa ṣubú léraléra

17 Níbẹ̀ ni wọn ó kígbe pé,

18 “Bí èmi ti wà láààyè,” ni ọba,

19 Ìwọ, ọmọbìnrin ti ń gbé Ejibiti

20 “Ẹgbọrọ abo màlúù tó lẹ́wà ní Ejibiti

21 Àwọn jagunjagun rẹ̀

22 Ejibiti yóò pòṣé bí ejò tí ń sá

23 Wọn o gé igbó rẹ̀ lulẹ̀,” ni Olúwa wí,

24 A ó dójútì ọmọbìnrin Ejibiti,

25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí pé: “Èmi yóò rọ̀jò ìyà mi sórí Amoni òrìṣà Tebesi, sórí Farao, sórí Ejibiti àti àwọn òrìṣà rẹ̀ àti sórí àwọn ọba rẹ̀ àti sórí àwọn tó gbẹ́kẹ̀lé Farao.

26 Èmi ó sì fi wọ́n lé àwọn tó wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́, lé Nebukadnessari ọba Babeli, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Ejibiti yóò sì di gbígbé bí i ti àtijọ́,” ni Olúwa wí.

27 “Má bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

28 Má bẹ̀rù, Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado