Jó 8

YOR

1 Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, sì dáhùn wí pé,

2 “Ìwọ yóò ti máa sọ nǹkan wọ̀nyí pẹ́ tó?

3 Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí?

4 Nígbà tí àwọn ọmọ rẹ̀ ṣẹ̀ sí i,

5 Bí ìwọ bá sì ké pe Ọlọ́run ní àkókò,

6 Ìwọ ìbá jẹ́ mímọ, kí ó sì dúró ṣinṣin:

7 Ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ ìbá tilẹ̀ kéré si í,

8 “Èmi bẹ̀ ọ́ ǹjẹ́, béèrè lọ́wọ́ àwọn ará ìgbà nì

9 Nítorí pé ọmọ-àná ni àwa, a kò sì mọ nǹkan,

10 Àwọn kì yóò wa kọ ọ́, wọn kì yóò sì sọ fún ọ?

11 Papirusi ha lè dàgbà láìní ẹrẹ̀

12 Nígbà tí ó wà ní tútù, tí a kò ké e lulẹ̀,

13 Bẹ́ẹ̀ ni ipa ọ̀nà gbogbo àwọn tí ó gbàgbé Ọlọ́run,

14 Àbá ẹni tí a ó kèé kúrò,

15 Yóò fi ara ti ilé rẹ̀, ṣùgbọ́n kì yóò lè dúró,

16 Ó tutù bí irúgbìn tí a bomirin níwájú oòrùn,

17 Gbòǹgbò rẹ̀ ta yí ebè ká,

18 Bí ó bá sì pa á run kúrò ní ipò rẹ̀,

19 Kíyèsi i, ayé rẹ̀ gbẹ dànù

20 “Kíyèsi i, Ọlọ́run kì yóò ta ẹni òtítọ́ nù,

21 títí yóò fi fi ẹ̀rín kún ọ ní ẹnu,

22 ìtìjú ní a o fi bo àwọn tí ó kórìíra rẹ̀,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado