1 “Ó jẹ́ pé nísinsin yìí bí ẹnìkan bá wà tí yóò dá wa lóhùn?
2 Nítorí pé ìbínú pa aláìmòye,
3 Èmi ti rí aláìmòye ti ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lulẹ̀,
4 Àwọn ọmọ rẹ̀ kò jìnnà sí ewu,
5 Ìkórè oko ẹni tí àwọn tí ebi ń pa sọ̀ di jíjẹ,
6 Bí ìpọ́njú kò bá ti inú erùpẹ̀ jáde wá ni,
7 Ṣùgbọ́n a bí ènìyàn sínú wàhálà,
8 “Ṣùgbọ́n bí ó ṣe tèmi, ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ní èmi yóò ti ṣìpẹ̀,
9 Ẹni tí ó ṣe ohun tí ó tóbi tí a kò lè ṣe àwárí,
10 Tí ń rọ̀jò sí orí ilẹ̀ ayé
11 Láti gbé àwọn orílẹ̀-èdè lékè
12 Ó yí ìmọ̀ àwọn alárékérekè po,
13 Ó mú àwọn ọlọ́gbọ́n nínú àrékérekè ara wọn,
14 Wọ́n sáré wọ inú òkùnkùn ní ọ̀sán;
15 Ṣùgbọ́n ó gba tálákà là ní ọwọ́ idà,
16 Bẹ́ẹ̀ ni ìrètí wà fún tálákà,
17 “Kíyèsi i, ìbùkún ni fún ẹni tí Ọlọ́run bá wí,
18 Nítorí pé òun a máa pa ni lára, síbẹ̀ òun a sì tún dì í ní ìdì ìtura,
19 Yóò gbà ọ́ nínú ìpọ́njú mẹ́fà,
20 Nínú ìyanu yóò gbà ọ́ lọ́wọ́ ikú
21 A ó pa ọ́ mọ́ kúrò lọ́wọ́ iná ahọ́n,
22 Ìwọ yóò rẹ́rìn-ín nínú ìparun àti ìyàn,
23 Nítorí pé ìwọ ti bá òkúta igbó mulẹ̀,
24 Ìwọ ó sì mọ̀ pé àlàáfíà ni ibùjókòó rẹ wà,
25 Ìwọ ó sì mọ̀ pẹ̀lú pé irú-ọmọ rẹ ó sì pọ̀
26 Ìwọ yóò wọ isà òkú rẹ ní ògbólógbòó ọjọ́,
27 “Kíyèsi i, àwa ti wádìí rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ní ó rí!