Jó 5

YOR

1 “Ó jẹ́ pé nísinsin yìí bí ẹnìkan bá wà tí yóò dá wa lóhùn?

2 Nítorí pé ìbínú pa aláìmòye,

3 Èmi ti rí aláìmòye ti ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lulẹ̀,

4 Àwọn ọmọ rẹ̀ kò jìnnà sí ewu,

5 Ìkórè oko ẹni tí àwọn tí ebi ń pa sọ̀ di jíjẹ,

6 Bí ìpọ́njú kò bá ti inú erùpẹ̀ jáde wá ni,

7 Ṣùgbọ́n a bí ènìyàn sínú wàhálà,

8 “Ṣùgbọ́n bí ó ṣe tèmi, ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ní èmi yóò ti ṣìpẹ̀,

9 Ẹni tí ó ṣe ohun tí ó tóbi tí a kò lè ṣe àwárí,

10 Tí ń rọ̀jò sí orí ilẹ̀ ayé

11 Láti gbé àwọn orílẹ̀-èdè lékè

12 Ó yí ìmọ̀ àwọn alárékérekè po,

13 Ó mú àwọn ọlọ́gbọ́n nínú àrékérekè ara wọn,

14 Wọ́n sáré wọ inú òkùnkùn ní ọ̀sán;

15 Ṣùgbọ́n ó gba tálákà là ní ọwọ́ idà,

16 Bẹ́ẹ̀ ni ìrètí wà fún tálákà,

17 “Kíyèsi i, ìbùkún ni fún ẹni tí Ọlọ́run bá wí,

18 Nítorí pé òun a máa pa ni lára, síbẹ̀ òun a sì tún dì í ní ìdì ìtura,

19 Yóò gbà ọ́ nínú ìpọ́njú mẹ́fà,

20 Nínú ìyanu yóò gbà ọ́ lọ́wọ́ ikú

21 A ó pa ọ́ mọ́ kúrò lọ́wọ́ iná ahọ́n,

22 Ìwọ yóò rẹ́rìn-ín nínú ìparun àti ìyàn,

23 Nítorí pé ìwọ ti bá òkúta igbó mulẹ̀,

24 Ìwọ ó sì mọ̀ pé àlàáfíà ni ibùjókòó rẹ wà,

25 Ìwọ ó sì mọ̀ pẹ̀lú pé irú-ọmọ rẹ ó sì pọ̀

26 Ìwọ yóò wọ isà òkú rẹ ní ògbólógbòó ọjọ́,

27 “Kíyèsi i, àwa ti wádìí rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ní ó rí!

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado