Jó 40

YOR

1 Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,

2 “Ẹni tí ń bá Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ní ẹ̀kọ́?

3 Nígbà náà ni Jobu dá Olúwa lóhùn wá ó sì wí pé,

4 “Kíyèsi i, ẹ̀gbin ni èmi—ohun kí ni èmi ó dà?

5 Ẹ̀ẹ̀kan ní mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi kì yóò tún sọ mọ́;

6 Nígbà náà ní Olúwa dá Jobu lóhùn láti inú ìjì àyíká wá, ó sì wí pé,

7 “Di àmùrè gírí ní ẹgbẹ́ rẹ bí ọkùnrin,

8 “Ìwọ ha fẹ́ mú ìdájọ́ mi di asán?

9 Ìwọ ni apá bí Ọlọ́run

10 Fi ọláńlá àti ọlá ìtayọ rẹ̀ ṣe ara rẹ ní ọ̀ṣọ́,

11 Mú ìrunú ìbínú rẹ jáde;

12 Wo gbogbo ìwà ìgbéraga, ènìyàn kí o sì rẹ ẹ sílẹ̀

13 Sin gbogbo wọn papọ̀ nínú erùpẹ̀,

14 Nígbà náà ní èmi ó yìn ọ́ pé,

15 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi Behemoti,

16 Wò o nísinsin yìí, agbára rẹ wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ,

17 Òun a máa jù ìrù rẹ̀ bí i igi kedari,

18 Egungun rẹ̀ ní ògùṣọ̀ idẹ,

19 Òun ni olórí nínú àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run;

20 Nítòótọ́ òkè ńlá ńlá ní i mu ohun jíjẹ fún un wá,

21 Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lótusì,

22 Igi lótusì síji wọn bò o;

23 Kíyèsi i, odò ńlá sàn jọjọ, òun kò sálọ;

24 Ẹnìkan ha lè mú un ní ojú rẹ̀,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado