Isaías 64

YOR

1 Ìwọ ìbá fa ọ̀run ya kí o sì sọ̀kalẹ̀ wá,

2 Gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí iná mú ẹ̀ka igi jó

3 Nítorí nígbà tí o bá ṣe àwọn ohun ẹ̀rù tí àwa kò nírètí,

4 Láti ìgbà àtijọ́ kò sí ẹni tí ó gbọ́ rí

5 Ìwọ a máa wá fún ìrànlọ́wọ́ àwọn tí wọn

6 Gbogbo wa ti dàbí ẹnìkan tí ó jẹ́ aláìmọ́,

7 Ẹnikẹ́ni kò pe orúkọ rẹ

8 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa.

9 Má ṣe bínú kọjá ààlà, ìwọ Olúwa,

10 Àwọn ìlú mímọ́ rẹ ti di aṣálẹ̀;

11 Tẹmpili mímọ́ ológo wa, níbi tí àwọn baba wa ti yìn ọ́,

12 Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí, Olúwa, ìwọ ó ha sì tún fi ara rẹ pamọ́ bí?

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado