1 Ìwọ ìbá fa ọ̀run ya kí o sì sọ̀kalẹ̀ wá,
2 Gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí iná mú ẹ̀ka igi jó
3 Nítorí nígbà tí o bá ṣe àwọn ohun ẹ̀rù tí àwa kò nírètí,
4 Láti ìgbà àtijọ́ kò sí ẹni tí ó gbọ́ rí
5 Ìwọ a máa wá fún ìrànlọ́wọ́ àwọn tí wọn
6 Gbogbo wa ti dàbí ẹnìkan tí ó jẹ́ aláìmọ́,
7 Ẹnikẹ́ni kò pe orúkọ rẹ
8 Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa.
9 Má ṣe bínú kọjá ààlà, ìwọ Olúwa,
10 Àwọn ìlú mímọ́ rẹ ti di aṣálẹ̀;
11 Tẹmpili mímọ́ ológo wa, níbi tí àwọn baba wa ti yìn ọ́,
12 Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí, Olúwa, ìwọ ó ha sì tún fi ara rẹ pamọ́ bí?