Isaías 63

YOR

1 Ta nì eléyìí tí ó Edomu wá,

2 Èéṣe tí aṣọ yín fi pupa

3 “Èmi nìkan ti dá tẹ ìfúntí wáìnì;

4 Nítorí ọjọ́ ẹ̀san wà ní ọkàn mi

5 Mo wò, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan láti ṣe ìrànwọ́.

6 Mo tẹ orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀ nínú ìbínú mi;

7 Èmi yóò sọ nípa àánú Olúwa,

8 Ó wí pé, “Lóòtítọ́ ènìyàn mi ni wọ́n,

9 Nínú gbogbo ìpọ́njú wọn, inú òun pẹ̀lú bàjẹ́

10 Síbẹ̀síbẹ̀ wọ́n ṣọ̀tẹ̀

11 Lẹ́yìn náà ni àwọn ènìyàn rẹ̀ rántí ọjọ́ ìgbà n nì,

12 ta ni ó rán apá ògo ti agbára rẹ̀

13 ta ni ó síwájú wọn la àwọn ọ̀gbun nì já?

14 gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ́ ẹran tí ó lọ sí pápá oko,

15 Bojú wolẹ̀ láti ọ̀run kí o sì rí i

16 Ṣùgbọ́n ìwọ ni baba wa,

17 Èéṣe Olúwa tí o fi jẹ́ kí a ṣáko kúrò ní ojú ọ̀nà rẹ

18 Fún ìgbà díẹ̀ ni àwọn ènìyàn rẹ fi gba ibi mímọ́ rẹ,

19 Àwa jẹ́ tìrẹ láti ìgbà n nì;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado