1 Ta nì eléyìí tí ó Edomu wá,
2 Èéṣe tí aṣọ yín fi pupa
3 “Èmi nìkan ti dá tẹ ìfúntí wáìnì;
4 Nítorí ọjọ́ ẹ̀san wà ní ọkàn mi
5 Mo wò, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan láti ṣe ìrànwọ́.
6 Mo tẹ orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀ nínú ìbínú mi;
7 Èmi yóò sọ nípa àánú Olúwa,
8 Ó wí pé, “Lóòtítọ́ ènìyàn mi ni wọ́n,
9 Nínú gbogbo ìpọ́njú wọn, inú òun pẹ̀lú bàjẹ́
10 Síbẹ̀síbẹ̀ wọ́n ṣọ̀tẹ̀
11 Lẹ́yìn náà ni àwọn ènìyàn rẹ̀ rántí ọjọ́ ìgbà n nì,
12 ta ni ó rán apá ògo ti agbára rẹ̀
13 ta ni ó síwájú wọn la àwọn ọ̀gbun nì já?
14 gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ́ ẹran tí ó lọ sí pápá oko,
15 Bojú wolẹ̀ láti ọ̀run kí o sì rí i
16 Ṣùgbọ́n ìwọ ni baba wa,
17 Èéṣe Olúwa tí o fi jẹ́ kí a ṣáko kúrò ní ojú ọ̀nà rẹ
18 Fún ìgbà díẹ̀ ni àwọn ènìyàn rẹ fi gba ibi mímọ́ rẹ,
19 Àwa jẹ́ tìrẹ láti ìgbà n nì;