1 Nítorí Sioni èmi kì yóò dákẹ́,
2 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò rí òdodo rẹ,
3 Ìwọ yóò sì jẹ́ adé dídán ní ọwọ́ Olúwa,
4 Wọn kì yóò pè ọ́ ní ìkọ̀sílẹ̀ mọ́
5 Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọkùnrin tí í gbé ọ̀dọ́mọbìnrin níyàwó,
6 Èmi ti fi olùṣọ́ ránṣẹ́ sórí odi rẹ ìwọ Jerusalẹmu;
7 àti kí ẹ má ṣe fún òun pẹ̀lú ní ìsinmi
8 Olúwa ti búra pẹ̀lú ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀
9 ṣùgbọ́n àwọn tí ó bá kóórè rẹ̀ ni yóò jẹ ẹ́,
10 Ẹ kọjá, ẹ kọjá ní ẹnu ibodè náà!
11 Olúwa ti ṣe ìkéde
12 A ó sì pè wọ́n ní Ènìyàn Mímọ́,