1 Ẹ̀mí Olúwa Olódùmarè wà lára mi
2 láti kéde ọdún ojúrere Olúwa
3 àti láti pèsè fún àwọn tí inú wọn bàjẹ́ ní Sioni
4 Wọn yóò tún àwọn ahoro àtijọ́ kọ́
5 Àwọn àjèjì ni yóò máa da ọ̀wọ́ ẹran rẹ;
6 A ó sì máa pè yín ní àlùfáà Olúwa,
7 Dípò àbùkù wọn
8 “Nítorí Èmi, Olúwa fẹ́ràn ìdájọ́ òdodo;
9 A ó mọ ìrandíran wọn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè
10 Èmi yọ̀ gidigidi nínú Olúwa;
11 Gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ ti í mú irúgbìn jáde