1 Olódodo ṣègbé
2 Gbogbo àwọn tí ń rìn déédé
3 “Ṣùgbọ́n ẹ súnmọ́ ìhìn-ín, ẹ̀yin ọmọ aláfọ̀ṣẹ,
4 Ta ni ó fi ń ṣẹlẹ́yà?
5 Ẹ gbinájẹ fún ìṣekúṣe láàrín igi óákù
6 Àwọn ère tí ó wà ní àárín òkúta dídán
7 Ìwọ ti ṣe ibùsùn rẹ lórí òkè gíga tí ó rẹwà;
8 Lẹ́yìn àwọn ìlẹ̀kùn yín àti òpó ìlẹ̀kùn yín
9 Ẹ̀yin lọ sí Moleki pẹ̀lú òróró olifi
10 Àwọn ọ̀nà yín gbogbo ti mú àárẹ̀ ba á yín,
11 “Ta ni ó ń pá yín láyà tí ń bà yín lẹ́rù
12 Èmi yóò ṣí òdodo yín páyà àti iṣẹ́ yín,
13 Nígbà tí ẹ bá kígbe fún ìrànlọ́wọ́
14 A ó sì sọ wí pé:
15 Nítorí èyí ni ohun tí Ẹni gíga àti ọlọ́lá jùlọ wí
16 Èmi kì yóò fẹ̀sùn kan ni títí láé,
17 Inú bí mi nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀kánjúwà rẹ̀;
18 Èmi ti rí ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, ṣùgbọ́n Èmi yóò wò ó sàn;
19 ní dídá ìyìn sí ètè àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ní Israẹli.
20 Ṣùgbọ́n àwọn ìkà dàbí i ríru Òkun
21 “Kò sí àlàáfíà fún àwọn ìkà,” ni Ọlọ́run mi wí.