Isaías 57

YOR

1 Olódodo ṣègbé

2 Gbogbo àwọn tí ń rìn déédé

3 “Ṣùgbọ́n ẹ súnmọ́ ìhìn-ín, ẹ̀yin ọmọ aláfọ̀ṣẹ,

4 Ta ni ó fi ń ṣẹlẹ́yà?

5 Ẹ gbinájẹ fún ìṣekúṣe láàrín igi óákù

6 Àwọn ère tí ó wà ní àárín òkúta dídán

7 Ìwọ ti ṣe ibùsùn rẹ lórí òkè gíga tí ó rẹwà;

8 Lẹ́yìn àwọn ìlẹ̀kùn yín àti òpó ìlẹ̀kùn yín

9 Ẹ̀yin lọ sí Moleki pẹ̀lú òróró olifi

10 Àwọn ọ̀nà yín gbogbo ti mú àárẹ̀ ba á yín,

11 “Ta ni ó ń pá yín láyà tí ń bà yín lẹ́rù

12 Èmi yóò ṣí òdodo yín páyà àti iṣẹ́ yín,

13 Nígbà tí ẹ bá kígbe fún ìrànlọ́wọ́

14 A ó sì sọ wí pé:

15 Nítorí èyí ni ohun tí Ẹni gíga àti ọlọ́lá jùlọ wí

16 Èmi kì yóò fẹ̀sùn kan ni títí láé,

17 Inú bí mi nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀kánjúwà rẹ̀;

18 Èmi ti rí ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, ṣùgbọ́n Èmi yóò wò ó sàn;

19 ní dídá ìyìn sí ètè àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ní Israẹli.

20 Ṣùgbọ́n àwọn ìkà dàbí i ríru Òkun

21 “Kò sí àlàáfíà fún àwọn ìkà,” ni Ọlọ́run mi wí.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado