1 Èyí ni ohun ti Olúwa sọ:
2 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó ṣe èyí,
3 Má ṣe jẹ́ kí àjèjì kan tí ó ti di ara rẹ̀
4 Nítorí pé báyìí ni Olúwa wí:
5 fún wọn ni Èmi yóò fún nínú tẹmpili àti àgbàlá rẹ̀
6 Àti àwọn àjèjì tí ó so ara wọn mọ́ Olúwa
7 àwọn wọ̀nyí ni èmi yóò mú wá òkè mímọ́ mi,
8 Olúwa Olódùmarè sọ wí pé—
9 Ẹ wá, gbogbo ẹ̀yin ẹranko inú pápá,
10 Àwọn olùṣọ́ Israẹli fọ́jú,
11 Wọ́n jẹ́ àwọn ajá tí ó kúndùn púpọ̀;
12 Igbe ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn ni wí pé, “Wá, fún mi ní ọtí wáìnì!