1 “Ẹ wá, gbogbo ẹ̀yin tí òǹgbẹ ń gbẹ,
2 Èéṣe tí ẹ fi ń ná owó fún èyí tí kì í ṣe àkàrà
3 Tẹ́tí sílẹ̀ kí o sì wá sọ́dọ̀ mi;
4 Kíyèsi i, mo ti fi òun ṣe ẹlẹ́rìí fún àwọn ènìyàn,
5 Lóòtítọ́ ìwọ yóò ké sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò mọ̀
6 Ẹ wá Olúwa nígbà tí ẹ lè rí i;
7 Jẹ́ kí ìkà kí ó kọ ọ̀nà rẹ̀ sílẹ̀
8 “Nítorí èrò mi kì í ṣe èrò yín,
9 “Gẹ́gẹ́ bí ọ̀run ti ga ju ayé lọ,
10 Gẹ́gẹ́ bí òjò àti yìnyín
11 bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ mi tí ó jáde láti ẹnu mi wá;
12 Ẹ̀yin yóò jáde lọ ní ayọ̀
13 Dípò igi ẹ̀gún ni igi junifa yóò máa dàgbà,